Font Size
Esekiẹli 22:21
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Esekiẹli 22:21
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
21 Èmi yóò kó yín jọ, èmi o sì fín iná ìbínú mi si yin lára, ẹ o si di yíyọ́ láàrín rẹ̀.
Read full chapter
Esekiẹli 23:9
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Esekiẹli 23:9
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
9 “Nítorí náà mo fi i sílẹ̀ fún àwọn olólùfẹ́ rẹ̀, ará Asiria, tí ó ní ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí i.
Read full chapter
Lefitiku 19:34
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Lefitiku 19:34
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
34 kí àjèjì tí ń gbé pẹ̀lú yín dàbí onílé láàrín yín kí ẹ sì fẹ́ràn rẹ̀ bí i ara yín, torí pé ẹ̀yin ti jẹ́ àjèjì ní ilẹ̀ Ejibiti rí. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.